top of page
Search

EJIOGBE

  • Writer: Awo Ifasola Sangobolade
    Awo Ifasola Sangobolade
  • 1 day ago
  • 1 min read


And the importance of not allowing unseen forces to consume one's success.


ree



Abẹ̀ ṣè mírìn, abẹ̀ pàní lọ́wọ́


Èjì ilèbè kò ṣe dí péfọ̀n


Adífá Ẹrẹ tí ti n jẹ ọmọ aráyé


Adífá fún Òrúnmìlà, baba ló ń jẹ èrè


Wọ́n kì ó kára n’lé ẹbọ ní kí ó má múṣé


Ó ti pé t’Ẹrẹ́ ti ń jẹ wa o


Àwa náà ò sì wá jẹ èrè





English Translation:


Improper handling of a knife leads to injury


Even two dull blades cannot pierce through a thick hide


Ifá was cast for Ere, who had been consuming human wealth


Ifá was also cast for Òrúnmìlà, the one who deserves the profit


They were advised to make ẹbọ so it would not be in vain


For a long time, Ere had been consuming what belonged to us


Now, it is our turn to enjoy the profit




Message:

This Ifá verse explains a time when the entity called Ere was consuming all the profits of humanity. Òrúnmìlà intervened through Ifá divination and was advised to perform ẹbọ (sacrifice). After doing so, the balance was restored, and humans began to benefit from their labor. The story encourages sacrifice, strategic spiritual alignment, and the importance of not allowing unseen forces to consume one's success.



 
 
 

Comments


bottom of page